O
Òyèkù Ògundà Excerpt
Odu Ifa Sacred Divination Pattern
The sacred Odu marks as cast on the Opele or Ikin divination tray
1
Ese Kinni
Ese Kinni
Ese — Yoruba Verse
Atorinla abidi gbdagi
adifafun fojonda tii somo aja niwarun
Igba ti n be laarin ota
✦
Ase — Ifa Spiritual Message (Yoruba)
Ifa ni ki eleyii o rubo nitori pe laarin ota ni o wa, ki o le baa segun gbogbo won.
Ebo — Sacrifice (Yoruba)
Akuko adire kan
Abo adie kanEyelekan
Epo pupa
Agbado
Owo
2
Ese Keji
Ese Keji
Ese — Yoruba Verse
Elegede ni n sawo inu igbo
Eremi ni n sawo awujaale
Adifafun folunlawe ti n je laarin ota
✦
Ase — Ifa Spiritual Message (Yoruba)
Ifa ni ki eleyii o rubo toripe aarin ota ni eleyii wa, pe ki eleyii o si se saara fun oku orun re ko le baa ni isegun.
Ebo — Sacrifice (Yoruba)
Ewe segun sete ni isale igba ebo
Akuko adire meji
Epo pupa
Agbado
Owo
3
Ese Keta
Ese Keta
Ese — Yoruba Verse
Bebe o kehin
Bebe oke oun
Adifafun Orisa nla oseremagbo
Ti o n sunkun pe oun o foju
bare Ebo ni won ni ko se
O si gbebo nibe o rubo
Morire nile
Mo rire lode
Ire to sonu, ire wole de
✦
Ase — Ifa Spiritual Message (Yoruba)
Ifa ni oore aje n bo lati okeere wa fun eleyii ati nibi ti eleyii ti n gbe pe o n saroye pe oun ko lowo lowo, pe ko rubo pe ire aje n bow a fun un.
Ebo — Sacrifice (Yoruba)
Igbin merinEyelefunfun meji
Epo
Eko
Obi merin
Agbado
Owo
4
Ese Kerin
Ese Kerin
Ese — Yoruba Verse
Oriri mori awo oba
Adifafun Oba
Ti n fomi oju sogbere aje sururu
✦
Ase — Ifa Spiritual Message (Yoruba)
Ifa loju aje n pon eleyii pe ko rubo, ko si fi ogede ominin, eyin, ekuru funfun bo aje, aje yoo joko ti eleyii.
Ebo — Sacrifice (Yoruba)
Opolopo eran ogedeEyelemeji
Opolopo oeo
Agbado
Explore Ifa
Oyeku Ogunda is one of the 256 sacred Odu Ifa — the corpus of divination verses that forms the foundation of the BODE Oracle system. Each Odu contains multiple Ese (verses) alongside their Ase (spiritual power), Ebo (sacrifice), and Akose (alchemical remedies).
Odus that share the same family or pairing include:Oyeku Meji,Oyeku Ogbe,Oyeku Iwori,Oyeku Odi.
Reflections & Testimonies
Be the first to share a reflection on Oyeku Ogunda Odu.
